-
1 Sámúẹ́lì 25:30Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
30 Tí Jèhófà bá ti ṣe gbogbo ohun rere tí ó ṣèlérí fún olúwa mi, tí ó sì fi ọ́ ṣe olórí Ísírẹ́lì,+
-
-
2 Sámúẹ́lì 6:21Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
21 Ni Dáfídì bá sọ fún Míkálì pé: “Iwájú Jèhófà ni mo ti ń ṣe àjọyọ̀, òun ni ó yàn mí dípò bàbá rẹ àti gbogbo agbo ilé rẹ̀ láti fi mí ṣe aṣáájú Ísírẹ́lì+ tó jẹ́ àwọn èèyàn Jèhófà. Torí náà, màá ṣe àjọyọ̀ níwájú Jèhófà,
-